Ija Ore Meji, Oriki Ijesa and Oriki Ibeji by Ogundare Foyanmu

Sdílet
Vložit
  • čas přidán 7. 09. 2024
  • Nínú àwo rẹ́kọ́ọ́dù yìí, Foyanmu kéwì lórí àwọn ẹ̀ka wọ̀nyí:
    ÌJÀ Ọ̀RẸ́ MÉJÌ
    ORÍKÌ ÌJẸ̀ṢÀ
    ORÍKÌ ÌBEJÌ
    ÌṢÒRO NÀÌJÍRÍÀ
    ỌMỌ ỌDẸ NÍ F'Ọ́MỌ ỌDẸ
    OLÓYÈ ADÉBÁYỌ̀ ALÁTA - BABALÁJÉ OGBOMOSO
    Bí ẹ bá fẹ́ mọ̀ sí i nípa Ogundare Foyanmu àti àwọn orin Ìjálá tó ti kọ pẹ̀lú ọ̀rọ̀ wọn, ẹ ríi pé ẹ ra ìwé tí 'ṢAYỌ̀ ALÁGBÈ kọ tí a pè ní ÌJÁLÁ OGUNDARE FOYANMU (ÌJÌNLẸ̀ ÈDÈ OHÙN ẸNU YORÙBÁ).
    For more information about Ogundare Foyanmu and insight into his Aré Ìjálá Ọdẹ, make sure you buy a book written by 'ṢAYỌ̀ ALÁGBÈ called ÌJÁLÁ OGÚNDÁRE FỌ́YÁNMU (ÌJÌNLẸ̀ ÈDÈ OHÙN ẸNU YORÙBÁ)
    AIF MEDIA is where we tune lives with tongue and culture. AIF MEDIA is a medium with passion to unite Yorùbá people to their heritage; promote and preserve godly virtues from Yorùbá culture, tradition and lifestyle; and give poetic admonitions.
    Our networks:
    YÒRÙBÁDÙNLÉDÈ | ÌTUMỌ̀ | BIBLICOPOETRY
    Enjoy our educational videos!
    To learn more about us, please visit our website.
    FACEBOOK
    bit.ly/AIFMEDI...
    TWITTER
    bit.ly/AIFMEDI...
    INSTAGRAM
    bit.ly/AIFMEDI...
    Watch, subscribe and share with others.
    #aifmedia #ijala #foyanmu #ogbomoso #sayoalagbe #ogundarefoyanmu #yorubapoetry #yorubaliterature #yorubaresearch #yorubapoem #ewi #areode #odale #ore

Komentáře • 8

  • @kunminiyi5063
    @kunminiyi5063 Před rokem +2

    Nice Yoruba language beauty

    • @aifmedia
      @aifmedia  Před rokem

      Bẹ́ẹ̀ni. Ẹwà èdè Yorùbá ni ti Ògúndáre Fọ́yánmu.
      Thanks for joining us. Blessings!

  • @hamzatjamiu4926
    @hamzatjamiu4926 Před rokem +1

    So beautiful

    • @aifmedia
      @aifmedia  Před rokem

      Yes... Thanks for joining us.
      Ẹ ṣeun.

  • @hamzatjamiu4926
    @hamzatjamiu4926 Před rokem +1

    Fantastic

    • @aifmedia
      @aifmedia  Před rokem

      Thanks for joining us here.
      A dúpẹ́ púpọ̀.

  • @adelakinagbonbioka2696
    @adelakinagbonbioka2696 Před 10 měsíci

    Could you please share a link for the book you referenced in the description?

    • @aifmedia
      @aifmedia  Před 10 měsíci

      I am sorry, this book is not on digital stores. It's only available for local orders.
      The author is 'Ṣayọ̀ Àlàgbé from Ògbómọ̀ṣọ́, Nigeria.